BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ipinlẹ Oyo
A ní ìwé ilẹ̀ ìjọba, síbẹ̀, ìjọba Oyo fẹ́ lé wa lórí ilẹ̀ wá- Ọ̀kan lára àwọn tọ́rọ̀ kàn
29 Bélú 2025
Ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fọ́kùnrin márùn ún tó dáwọ́ jọ lu awakọ̀ 'taxi' pa n'Ibadan
26 Bélú 2025
Èébú àti èpè tí ẹ fi ń ránṣẹ́ kò tu irun kankan lára mi, mò ń bọ̀ wá bá ẹ̀yin tí ẹ̀ ń dín àkàrà lójú pópó torí mi, a dìjọ máa jẹ àkàrà náà ni - Makinde
25 Bélú 2025
Mi ò lérò pé mo lè kọ́lé mọ́ láyé lẹ́yìn tí mo ti pé ọdún 70, kí n tó jẹ ilé tó rẹwà níbi àjọ̀dún iléeṣẹ́ redio Ayefele - Màmá Aminat
18 Bélú 2025
Ta ni Kabiru Tanimu Turaki tí wọ́n yàn bíi alága ẹgbẹ́ òṣèlú PDP
17 Bélú 2025
Wọ́n pè mí ní olè, ajagungbalẹ̀ lórí ọ̀nà Circular Road àmọ́ mi ò jẹ ẹnìkankan ní àlàyé - Makinde
12 Bélú 2025
Ọba Ladoja ké sí Trump láti yọwọ́ kúrò lọ́rọ̀ Nàíjíríà torí agbéṣùmọ̀mí kò mọ ìyàtọ̀ láàrin Mùsùlùmí àti Kristẹni
10 Bélú 2025
Ṣé lóòótọ́ ni àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lu olùkọ́ pa ní ìlú Ogbomoso?
8 Bélú 2025
EFCC dá ilé, ọkọ̀ àti dúkìá míì padà fún ẹni tí Abọrẹ̀ kan lù ní jìbìtì n‘Ibadan èyí tó lé ní ₦200m
30 Ọ̀wàrà 2025
Ọlọ́pàá àti èèyàn kan fara gbọta báwọn adigunjalè ṣe kọlu ọkùnrin kan tó lọ gbá owó ní Báńkì n‘Ibadan
28 Ọ̀wàrà 2025
Iléẹjọ́ ti dá wa láre, mó ń padà sí gáréèjì bíi alága NURTW l‘Oyo lẹ́yìn ìdádúró ọ̀dún mẹ́fà àmọ́ a kò ní fa wàhálà - Ejiogbe
27 Ọ̀wàrà 2025
3:39
Fídíò,
Àwòkọ́ṣe ni mo jẹ́ fún aráàlú, àwọn ohun àmúyangàn ni mo máa ń ṣe -Alaafin Oyo
, Duration 3,39
27 Ọ̀wàrà 2025
"Ìgbà tí mo wà l'ọ́mọdé ni a ti gbádùn iná ọba gbẹ̀yìn n'Ibarapa" - Eleruwa
25 Ọ̀wàrà 2025
Olubadan Ladoja kọminú lórí iléeṣẹ́ tó ń kógbáwọlé nílùú Ibadan, wo àwọn àwọn èèkàn tó gbé kalẹ̀ láti ṣàtúnṣe ọrọ̀ ajé rẹ̀
25 Ọ̀wàrà 2025
Ṣé lóòótọ́ nìjọba Seyi Makinde bẹ́rẹ́ owó orí gbígbá lórí ayẹyẹ ìsìnkú, ìsọmọlórúkọ, ìgbéyàwó àtàwọn ayẹyẹ míràn l'Oyo?
23 Ọ̀wàrà 2025
Púpọ̀ nínú ọọ́físì ìjọba ìbílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo ló ti dagẹgẹ, Makinde gbọdọ̀ ṣe àtúnṣe si – Àwọn àṣofin
20 Ọ̀wàrà 2025
Àwọn wo ni àgbà amòfin márùn-ún tí Olubadan Ladoja gba láti gbógun ti àwọn ajagungbalẹ̀ n'Ibadan?
18 Ọ̀wàrà 2025
"Digbí ni PDP wà, bí àwọn gómìnà kan ṣe fi ẹgbẹ́ sílẹ̀ kò tu irún kankan lára ẹgbẹ́ wa"
17 Ọ̀wàrà 2025
Kí ló kàn báyìí lẹ́yìn tí ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn wọ́gilé òfin tí Makinde fi de ẹgbẹ́ NURTW l'Oyo?
6 Ọ̀wàrà 2025
6:44
Fídíò,
Ojú oorun ni Aláàfin ti jí mi pé wọ́n ti yan òun ní ọba, n kò mọ pé ìdílé ọba ló ti wá ká tó ṣe ìgbéyàwó - Ayaba Alaafin
, Duration 6,44
4 Ọ̀wàrà 2025
Gani Adams, Aláàfin Oyo, Afẹnifẹre korò ojú sí ìpànìyàn ní Kwara, dábàá ààbò fún ilẹ̀ Yorùbá
3 Ọ̀wàrà 2025
Kí ló dé tí ẹnu ń kun Taye Currency lẹ́yìn ayẹyẹ ìgbadé Olubadan Ladoja?
29 Owewe 2025
4:01
Fídíò,
Èyí ni iye àkàsọ̀ tí Oludije sípò Olubadan yóò gun, kò tó dé orí ìtẹ́
, Duration 4,01
26 Owewe 2025
Wo àwọn nǹkan tó ti wáyé nílùú Ibadan ṣáájú ìfinijoyè Ọba Ladoja
25 Owewe 2025
Ìṣájú
Page
8
nínú
40
1
5
6
7
8
9
10
11
40
Tókàn