BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Eto Iselu
3:33
Fídíò,
Ìpínlẹ̀ Osun kò nílò ẹ̀jẹ̀ ẹnikẹ́ni láti tẹ̀ síwájú, ẹ̀yin olóṣèlú tó ń pa èèyàn, ẹ jáwọ́ níbẹ̀ – Olùdíje gómìnà ZLP
, Duration 3,33
7 Ògún 2026
Mo bẹ gómìnà Imo láti gba àláàfíà láàyè lásìkò ìbò gómìnà l‘Osun, kó sì rántí pé ọmọ ìpínlẹ̀ Imo ni aya mi - Davido
6 Ògún 2026
3:38
Fídíò,
À ti tún àwọn ẹ̀rọ̀ BVAS wa ṣe láti dènà kí èèyàn kan lo káàdì ìdìbò ẹlòmíràn nínú ìdìbò gómìna l‘Osun - Alága INEC
, Duration 3,38
4 Ògún 2026
Àwọn jàndùkú kọlu ìyàwó Bola Oyebamiji lẹ́yìn ìpolongo ìbò nílùú Ede, ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí
3 Ògún 2026
Kí ló fa rògbòdìyàn láàrín Bísọ̀ọ̀bù Onaiyekan àti ìjọba apapọ, tí wọn ṣe ń sọ̀kò ọ̀rọ̀ síra wọn?
3 Ògún 2026
Nǹkan mẹ́wàá pàtàkì tí máà ṣe fún aráàlú bí mo bá di gómìnà Osun rèé- Iwaloye
1 Ògún 2026
6:03
Fídíò,
Mo máa ṣiṣẹ́ tayọ Gómìnà Adeleke àtàwọn olùdíje yòókù tí mo bá wọlé ìbò Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun - Olùdíje AAC
, Duration 6,03
31 Agẹmo 2026
Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ l'Osun ṣáájú ìbò gómìnà tó ń bọ̀, ọlọ́pàá mú akọ̀wé ijọba, Adeleke ní aráàlú kò ní gbà
30 Agẹmo 2026
Wo ohun tí ìdájọ́ ilé ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn tó ní INEC dá orúkọ ẹgbẹ́ márùn-ún padà túmọ̀ sí fún Adeleke, Oriyomi
29 Agẹmo 2026
Mo wà nínú ilé nígbà táwọn DSS ń yìnbọn lákọ lákọ láti pa mí, àmọ́ wọn ò rí mi - Sunday Igboho
29 Agẹmo 2026
A kò tí ì fún PFIPC ní kọ́bọ̀ nínú ₦1.3bn tí wọ́n yà sọ́tọ̀ fún un - Ọ́fíìsì ètò ìṣúná
26 Agẹmo 2026
Tinubu àti Atiku tún gbéná wojú ara wọn lórí ìgbẹ́jọ́ Tinubu tí iléeṣẹ́ kan gbé dìde ní Amẹ́ríkà
26 Agẹmo 2026
Ìbanilórúkọjẹ́ lẹ̀sùn ìkówójẹ tí wọ́n fi kàn mí, Oluomo sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tílé aṣòfin Ogun fagilé ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan adarí ilé tẹ́lẹ̀
25 Agẹmo 2026
Wo àwọn àyípadà tó máa wáyé sí ètò ààbò bí Ààrẹ Tinubu ṣe buwọ́lu àfikún ẹkùn iléeṣẹ́ ológun di méjìlá
24 Agẹmo 2026
Nǹkan mẹ́wàá ni mo ní àfojúsùn láti mójútó tí mo bá di gómìnà Osun - Najeem Salaam
24 Agẹmo 2026
Obasanjo àti Osoba sọ òkò ọ̀rọ̀ síra wọn lórí ìbò 2003, àṣírí ọ̀pọ̀ ìpàdé ìdákọ́ńkọ́ tú àti ìdí táwọn gómínà AD ṣe pàdánù sọ́wọ́ PDP
24 Agẹmo 2026
Ìwádìí BBC rèé lórí ẹ̀sùn àjẹbánu ₦44m táwọn aṣòfin Ondo fi kan Olórí ilé tí wọ́n fi ni kó fipò sílẹ̀
24 Agẹmo 2026
Ilé ìgbìmọ̀ Aṣojú-ṣòfin buwọ́lu àbádòfin fún ìdásílẹ̀ ọlọ̀pàá ìpínlẹ̀ lórílẹ̀èdè Nàìjíríà
23 Agẹmo 2026
Iyabo Obasanjo àti olùdíje sípò gómìnà lẹ́gbẹ́ APC l‘Ogun, Yayi, ń tutọ́ síra wọn lójú
21 Agẹmo 2026
5:06
Fídíò,
Igun méjì ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò dá rògbòdìyàn sílẹ̀ l'Osogbo, ìbọn ń dún lákọlákọ, aráàlú ń sá kiri
, Duration 5,06
21 Agẹmo 2026
Wo àwọn nǹkan tí Andy Burnham, Olóòtú ìjọba UK tuntun lóun yóò ṣe fún ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì
20 Agẹmo 2026
Ta ni Andy Burnham tó fẹ́ di Olóòtú Ìjọba Ilẹ̀ Gẹ́ẹ̀sì tuntun?
18 Agẹmo 2026
Ohun tí a mọ̀ nípa ikú ọ̀dọ́bìnrin Mary Habila, òṣíṣẹ́ Mínísítà David Umahi tí wọ́n ló kú sílé rẹ̀
18 Agẹmo 2026
6:21
Fídíò,
Ìpinnu mi láti di gómìnà ìpínlẹ̀ Osun jẹ́ kádàrá èmi àti Ọlọ́run – Bola Oyebamiji olùdíje APC
, Duration 6,21
17 Agẹmo 2026
Ìṣájú
Page
2
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
8
40
Tókàn