BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ileesẹ Ologun
Ìjọba gbọ́dọ̀ ní àkójọpọ̀ orúkọ gbogbo aráàlú lórí ẹ̀rọ kọ̀mpútà tó bá fẹ́ rẹ́yìn ìgbésùnmọ̀mí - Christopher Musa
5 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Àkójọpọ̀ ìkọlù tó ti ṣẹlẹ̀ ní Naijiria lẹ́yìn tí Tinubu kéde ìlú ò fararọ lẹ́ka ètò ààbò
2 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Àwọn agbébọn tún ṣèkọlù sí Eruku ní Kwara, jí àgbẹ̀ kan gbé lọ lẹ́yìn ìkọlù ilé ìjọ́sìn CAC
1 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Abẹ ìsẹjọba rẹ gẹ́gẹ́ bí ààrẹ ni ìgbésùnmọ̀mí ti bẹ̀rẹ̀- Iléeṣẹ́ Ààrẹ fèsì padà fún Obasanjo
1 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Àwọn jàndùkú agbébọn tún ya wọ ṣọ́ọ̀ṣì Kerubu (C&S) ní Kogi, jí pásítọ̀ àti ìyàwó rẹ̀ pẹ̀lú àwọn èèyàn míì gbé lọ
30 Bélú 2025
Ológun wọ́gilé èsì ìbò ààrẹ ní Guinea-Bissau lẹ́yìn ìdìtẹ̀gbàjọba, kéde ọ̀gágun N'Tam gẹ́gẹ́ bí olórí, AU, ECOWAS fọnmú
28 Bélú 2025
Akẹ́kọ̀ọ́ mọ̀kànlá nínú 303 tilé ẹ̀kọ́ St Mary Catholic ní Niger bọ́ lọ́wọ́ agbebọn, bí Gómìnà Kebbi ṣe fẹ́ fa akẹ́kọ̀ọ́ 24 tó dé láti ọ̀dọ̀ ajínigbé, lé òbí wọn lọ́wọ́
26 Bélú 2025
Kí ni ìtúmọ̀ ìlànà 'non-kinetic' tí ìjọba ní òun fi dúnàádúrà gba àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Kebbi àti olùjọ́sìn Eruku lọ́wọ́ àwọn ajínigbé?
26 Bélú 2025
Ẹ̀yin ológun, ẹ gbákoso, rọ̀gbà yí àwọn igbó ọba tó wà ní Kwara, Niger àti Kebbi ká, ẹ gba àwọn tó wà ní ìgbèkùn ajínigbé kalẹ̀ - Tinubu
26 Bélú 2025
Orílẹ́èdè Afirika mẹ́wàá tí ìjọba ti náwó jùlọ lórí ètò ààbò lọ́dún 2025
22 Bélú 2025
Ààrẹ Tinubu bá ẹbí Ọgagun Uba táwọn agbébọn pa kẹ́dùn
19 Bélú 2025
Olórí ikọ̀ aláàbò tẹ́lẹ̀, Lucky Irabor àti Mínísítà ètò ààbò ìpínlẹ̀, Bello Matawalle, ní Wike ti ṣẹ̀ sí Ààrẹ Naijiria nitori aáwọ̀ òun àti ṣọ́jà
17 Bélú 2025
Obasanjọ àti Danjuma ti pè mí rí lórí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ l'Abuja, wọn kò fi ológun halẹ̀ mọ́ mi – Wike
14 Bélú 2025
Ohun tó fa ikú èèyàn mẹ́fà àti ọ̀pọ̀ tó farapa lásìkò tí wọ́n fẹ́ gba iṣẹ́ ológun ní Ghana rèé
13 Bélú 2025
Àlàyé rèé lórí bí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ tó fa aáwọ láàárín Wike àti ọmọ ológun ṣe jẹ́
13 Bélú 2025
''Wike jẹ̀bí pé ó pe ọmogun ní òmúgọ̀ àmọ́ iléeṣẹ́ ológun gbọdọ̀ dá ṣèríà fún ọmogun tó gbéná wojú Wike, káwọn ọmogun má ba à dáwọ́jọ lu mínísítà lọ́jọ́ kan''
12 Bélú 2025
Kí ni kókó ohun tí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Boko Haram àti ISWAP ń jà fún tí igba èèyàn ṣe tẹ́rí gbaṣọ́?
11 Bélú 2025
Ẹ̀sọ̀pẹ̀lẹ́ ló yẹ kóo fi dá sí ìpèníjà ààbò Nàìjíríà - Ìjọba àpapọ̀ rọ Trump
6 Bélú 2025
Kí làtunbọ̀tán àwọn orílẹ̀èdè méje tí Amẹ́ríkà ti kọ́mọ́ogun wọ̀ rí ní Áfíríkà?
5 Bélú 2025
Tinubu gbọdọ̀ sọ ìdí tó fi yọ àwọn ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ ológun Naijiria nípò, ẹgbẹ́ òṣèlú ADC yarí
26 Ọ̀wàrà 2025
Kà nípa àwọn ìdìtẹ̀gbàjọba ológun tó ti ṣẹlẹ̀ ní Naijiria àti ìpa tó ní
21 Ọ̀wàrà 2025
Ṣọ́jà la ìbọn mọ́ awakọ̀ kan lórí l'Ondo tó fi kú, iléeṣẹ́ ológun ṣàlàyé bí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe wáyé
18 Ọ̀wàrà 2025
''Ìdí tí a fi ń bẹ ìjọba láti gbà wá láyè kí á máa gbé ìbọn fún ra wa"
6 Ọ̀wàrà 2025
Ìdí rèé tí Sunday Igboho fi ṣàbẹ̀wò sí Ọba Ladoja àti ohun tó fẹ́
2 Ọ̀wàrà 2025
Ìṣájú
Page
5
nínú
20
1
2
3
4
5
6
7
8
20
Tókàn