BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ofin
Èèyàn 11mílíọ̀nù tí kò tíì so NIN wọn pọ̀ mọ́ nọ́mbà fóònù yóò já kúrò lórí ìlà ìpè lónìí
29 Èrèlè 2024
Àwọn agbébọn kọlu ọọ́físì iléeṣẹ́ ètò àbò Chad, ọ̀pọ̀ òkú sùn
28 Èrèlè 2024
Tinubu ṣetán àmúlò àbájáde ìgbìmọ̀ Oronsanye tó dàbá àtúntò ìṣàkóso ìjọba
26 Èrèlè 2024
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC, ẹ tún èrò yín pa lórí ìwọ́de tí ẹ fẹ́ ṣe - Mínísítà ètò ìdájọ́
25 Èrèlè 2024
Wo iye owó ti iléẹjọ́ gba béèlì gómìnà Kwara àná,Abdulfatah Ahmed lórí ẹ̀sùn màgòmágó
24 Èrèlè 2024
Ọkùnrin kan gbé iléeṣẹ́ tẹ́tẹ́ re ilé ẹjọ́ lẹ́yìn tí wọ́n ní àṣìṣe ni N510bn tó jẹ
24 Èrèlè 2024
Ìyàwó mi Ropo ni wọ́n lò láti mú mi ní Benin Republic - Sunday Igboho
24 Èrèlè 2024
EFCC yawọ Sabo n‘Ibadan, tí wọ́n ti n ṣẹ Dollar, ọwọ́ tẹ oníṣòwò mọ́kànlá
23 Èrèlè 2024
Ìṣòro tó ń kojú aráàlú pọ̀jù, ẹ má yọwó ìrànwọ́ tàbí gbé èlé gorí owó iná ọba – Ilé aṣòfin àpapọ̀
23 Èrèlè 2024
EFCC mú gómìnà àná ní Kwara lórí ẹ̀sùn màgòmágó N10bn, PDP ṣe ìwọ́de pé ìwà ìfìyàjẹni ni
22 Èrèlè 2024
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́, aráàlú àtàwọn òṣìṣẹ́ tú sí ìgboro láti ṣe ayẹyẹ ìkẹyìn fún Akeredolu
21 Èrèlè 2024
Kókó márùn-ún nípa bí ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ yóò ṣe máà ṣiṣẹ́ bó ṣe wà nínú àbá òfin ìdásílẹ̀ rẹ̀
21 Èrèlè 2024
7:06
Fídíò,
"Mo ṣẹ́ oyún oge torí ẹbí, ọ̀rẹ́ àti ṣọ́ọ̀ṣì pa mí tì, ilé ọmọ mi bàjẹ́, dókítà ní n kò le bímọ mọ́"
, Duration 7,06
20 Èrèlè 2024
Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ti ilé ìwòsàn aládàni mẹ́fà pa lórí ẹ̀sùn lílo ayédèrú òṣìṣẹ́
16 Èrèlè 2024
Wo bí ìgbẹ́jọ́ Saheed Shittu, tí àwọn Alfa fi ẹ̀sùn ìbanilórúkọ jẹ́ kàn ṣe lọ ní Ilorin
14 Èrèlè 2024
'Ẹ̀wọ̀n àti owó ìtanràn ń dúró dè ọ́ tó o bá fi ẹnu já wáyà lórí ayélujára'
13 Èrèlè 2024
Kí ló wà nínú òfin iná mọ̀nàmọ̀nà tuntun tí Ààrẹ Tinubu búwọ lù
10 Èrèlè 2024
Wo àwọn tó fẹ̀sùn olè kan Lizzy Anjorin, àti ohun tí ọlọ́pàá ń ṣe fún wọn lọ́wọ́lọ́wọ́
9 Èrèlè 2024
Ìjọba buwọ́lu òfin tó wọ́gilé ìdájọ́ ikú
8 Èrèlè 2024
Wo ohun tó lè ṣẹlẹ nítorí ìdìbò tí wọ́n sún síwájú ní Senegal
6 Èrèlè 2024
Èèyàn mẹ́rin kú, ọ̀pọ̀ farapa níbi ìjà àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn l’Abẹ́òkúta
6 Èrèlè 2024
EFCC ti gbé Olùdásílẹ̀ ìjọ, wọ́n ní o lu ọmọ ìjọ ní jìbìtì
6 Èrèlè 2024
8:07
Fídíò,
'Ńṣe ni ẹ̀jẹ̀ bo Pásítọ̀ Adegboyega lẹ́yìn tí àwọn darandaran náà gún un ní ọ̀bẹ'
, Duration 8,07
6 Èrèlè 2024
Darasimi Omoseyin rí ẹ̀wọ̀n he nítorí pé o tẹ owó náírà mọ́lẹ̀ lójú agbo lẹ́yìn tó ṣe náírà báṣubàṣu
2 Èrèlè 2024
Ìṣájú
Page
36
nínú
40
1
33
34
35
36
37
38
39
40
Tókàn