BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ẹsin igbagbọ
Ikú kò m'ọmọdé, kò màgbà, ẹ gbàdúrà fún ìdílé mi àti aya pẹ̀lú ọmọ olóògbé- Pásítọ̀ Adeboye
12 Èbibi 2021
Bó ṣe nípasẹ̀ ọkada ni tàbí ọkọ̀ ojú omi tàbí láti inú ihò ilẹ̀, ẹ wá ọ̀nà láti fi Naijiria sílẹ̀- Pasitọ Paul Adefarasin
11 Èbibi 2021
Ìjọ Kátólìkì, ẹ jèbùrẹ́, ọmọdé ló ṣe èmi àtàwọn ọmọ ìjọ mi- Father Mbaka
10 Èbibi 2021
À ń ṣe ìwádìí lọ́wọ́ bí ''candle'' ṣe pa Kayode Badru ní ìpínlẹ̀ Eko - Ọlọ́pàá
10 Èbibi 2021
Ẹ wo bí Leke Adeboye, àwọn ọ̀dọ́ ìjọ RCCG ṣe gẹ irun wọn láti bú ọlá fún Dare Adeboye tó papòdà
10 Èbibi 2021
Emmanuel Abina, ọmọ Olùdarí ìjọ GOFAMINT, Elijah Abina jáde láyé lẹ́yìn ikú ìyàwó rẹ̀
9 Èbibi 2021
A kò ní pe Ọlọ́run ní ẹjọ́ lórí ìkú ọmọ wa, Dare Adeboye - Ẹbí Adeboye
9 Èbibi 2021
Ìyàwó Adeboye gbàdúrà fún Nàìjíríà ní ìgbà akọkọ tó fara hàn lẹ́yìn ikú ọmọ wọn, Dare
8 Èbibi 2021
Ikú Dare Adeboye kò ní ǹkankan ṣe pẹ̀lú Covid-19, a bẹ̀bẹ̀ láti dá wà lákòókò yìí - Ẹbi Adeboye
7 Èbibi 2021
Ẹbí Adeboye kéde bí ìlànà ikú Pásítọ Dare yoo ṣe lọ
7 Èbibi 2021
Àwọn ǹkan tí o kò gbọ́ rí nípa Dare Adeboye tó kú
6 Èbibi 2021
Ọjọ́ 30 ni wọ́n fẹ́ fi gbé mi pamọ́, ariwo ọmọ ìjọ ló jẹ́ kí wọ́n tú mi sílẹ̀ - Father Mbaka
6 Èbibi 2021
Ìyá àláwo tó di àjíhìnrere òjijì fi àwọn òrìṣà rẹ̀ ṣe ẹlẹ́yà
3 Èbibi 2021
Ìjọ Islam fìwé pe Wòlíì Genesis bíi àlejò pàtàkì sí òru Lailatul Quadir, ariwo sọ
1 Èbibi 2021
Ìwàásù Baba Adeboye ló sọ mí di Kristẹni - Funke Etti
28 Ìgbé 2021
Wo oore tí Ramadan n ṣe fún àwọn ẹlẹ́sìn mìíràn tó n gbà á
28 Ìgbé 2021
Ọjọ́ Ajé gba ọ̀pọ̀ ẹ̀jẹ̀ ọmọ Nàíjíríà láti ọwọ́ àwọn agbébọn
27 Ìgbé 2021
Ẹ má dán abẹ́rẹ́ Covid-19 wò lára mi, mi ò gbà! Mi kìí ṣe ẹmọ́ òyìnbó- David Oyedepo
18 Ìgbé 2021
Wo àlàyé Peter Fatomilola lórí bó ṣe dàgbà nínú ìdílé tó n dífá, tó tún n lọ ṣọ́ọ́ṣì
17 Ìgbé 2021
Ìlẹ̀kẹ̀ otútú ọgbọ̀n, Ìrọ́kẹ́, àwa ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ náà fẹ́ káwọn ọmọ wa máa wọ lọ sílé ìwé - Elebuibon
9 Ìgbé 2021
Àrà kengé! Ṣọ́ọ̀ṣì Church of England fẹ́ dá ère idẹ Benin méjì padà sí Nàìjíríà
9 Ìgbé 2021
Genesis Global: Sáká lara Woli Israel Ogundipe dá, kìí ṣe àìlera ló mú kí wọn fi sílẹ̀ lẹ́wọ̀n
4 Ìgbé 2021
Tẹlifísàn pásítọ̀ Oyakhilome wọ gàù nílẹ̀ UK torí òfegè ìròyìn
1 Ìgbé 2021
4:57
Fídíò,
Ṣé òtítọ́ ni wọ́n fi ẹ̀jẹ̀ oyún inú po abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19?
, Duration 4,57
28 Ẹrẹ̀nà 2021
Ìṣájú
Page
19
nínú
24
1
16
17
18
19
20
21
22
23
24
Tókàn