BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ofin
Sẹ́nétọ̀ Osun wọ gàù lẹ́yìn tó ní kí àwọn alátìlẹyìn òun máa pa àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú Accord lọ́jọ́ ìbò
12 Ògún 2026
Àgbékalẹ̀ ètò agbófinró tí kò ní ṣe ojúṣàájú fún ẹnikẹ̀ni ni ìjọba ń fẹ́ – Fagbemi
8 Ògún 2026
Báwo ni àjọ ICPC tún ṣe ṣàwárí ilé-iṣẹ́ ayédèrú méjì míràn tí Adeyemi Adeniyi dá sílẹ̀?
7 Ògún 2026
Adeleke wọ́ báǹkì First Bank àti EFCC lọ sílé-ẹjọ́ lórí àkáǹtì ìjọba Osun tí wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé
7 Ògún 2026
Àlàyé rèé lórí ìdí tí báálé ilé ṣe ju ọmọ rẹ̀ méjì sílẹ̀ láti orí ilé alájà mẹ́ta, tó tún fẹ́ ju ìyá wọn náà tẹ̀le
5 Ògún 2026
Oriyomi Hamzat kò kópa nínú ìdìbò abẹ́nú Accord, ẹ yọ ọ́ kúrò bíi olùdíje gómìnà - Busari Gudugúdù wọ́ ẹgbẹ́ òṣèlu Accord àti INEC lọ sílé-ẹjọ́
4 Ògún 2026
PFIPC: Kìí ṣe Adeyemi nìkan ló ṣe ohun tí wọ́n fẹ̀sùn rẹ̀ kàn án, ọ̀pọ̀ èèyàn nínú ìjọba ló lọ́wọ́ si - Agbẹjọ́rò
3 Ògún 2026
Ìwádìí bẹ̀rẹ̀ lórí fídíò tó ṣàfihàn báwọn ọlọ́pàá kan ti ṣe ìkọlù sí ọ̀dọ́kùnrin tó ń ta góòlù l'Eko
2 Ògún 2026
Ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá gbé ọ̀gá ọlọ́pàá tuntun lọ sí ìpínlẹ̀ Osun ṣáájú ìdìbò gómìnà tó n bọ̀
1 Ògún 2026
Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ l'Osun ṣáájú ìbò gómìnà tó ń bọ̀, ọlọ́pàá mú akọ̀wé ijọba, Adeleke ní aráàlú kò ní gbà
30 Agẹmo 2026
Kílódé tí ọtí pẹlẹbè ṣì pọ̀ ní ìgboro bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìjọba ti gbẹ́sẹ̀ le?
29 Agẹmo 2026
Ọmọ Nàìjíríà míràn tún kú sọ́wọ́ ọlọ́pàá ní South Africa; Ìjọba Nàìjíríà fárígá, pè fún ìwádìí kíkún
27 Agẹmo 2026
5:16
Fídíò,
Àdó olóró àwọn ajínigbé pa Shuaibu aṣọ́gbóọba lásìkò tó ń lé àwọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ gbé ní Oriire, àwọn ẹbí rẹ̀ pariwo síta
, Duration 5,16
27 Agẹmo 2026
A kò tí ì fún PFIPC ní kọ́bọ̀ nínú ₦1.3bn tí wọ́n yà sọ́tọ̀ fún un - Ọ́fíìsì ètò ìṣúná
26 Agẹmo 2026
Ọlọ́pàá mẹ́rin tó bèèrè owó ẹ̀yìn lọ́wọ́ awakọ̀ lọ́nà márosẹ̀ Ọrẹ si Benin wọ gàù, ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí wọn
25 Agẹmo 2026
Ìbanilórúkọjẹ́ lẹ̀sùn ìkówójẹ tí wọ́n fi kàn mí, Oluomo sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tílé aṣòfin Ogun fagilé ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan adarí ilé tẹ́lẹ̀
25 Agẹmo 2026
Mo Bimpe lérí láti gbé àwọn tó ní Lateef Adedimeji kọ́ ni bàbá àwọn ọmọ rẹ̀ lọ sílé ẹjọ́
25 Agẹmo 2026
Ilé ẹjọ́ gba onídùúró Blessing CEO pẹ̀lu ₦20m lórí ẹ̀sùn jìbìtì ₦69.15m
24 Agẹmo 2026
APC àti Makinde ju òkò ọ̀rọ̀ lu ara wọn lórí ìdájọ́ ilé ẹjọ́ láti dènà EFCC láti ṣe ìwádìí ìṣúná Oyo
24 Agẹmo 2026
Ọlọ́pàá mẹ́rin tó gbégi dínà lójú pópó fi tipá gba rìbá N57,000 lọ́wọ́ ọ̀gá àjọ tó ń gbógun tìwà àjẹbánu, ICPC, ọ̀rọ̀ bẹ́yìn yọ
22 Agẹmo 2026
Ẹgbẹ́ àwọn Kristẹni tako òfin tó sọ ọ́ di èèwọ̀ láti máa wàásù nínú ọkọ̀ akérò
19 Agẹmo 2026
Afurasí tíṣà tí wọ́n ló lu akẹ́kọ̀ọ́ pa jọ̀wọ́ ara rẹ̀ fún ọlọ̀pàá
19 Agẹmo 2026
Aisha Achimugu, bọ̀rọ̀kìnní obìnrin tí iléẹjọ́ gbẹ́sẹ̀lé ẹ̀ṣọ́ ara àti ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí owó rẹ̀ tó ₦8.9bn lẹ́yìn tí EFCC fí ẹ̀sùn kíkọ́rọ̀ jọ lọ́nà èrú kàn án
17 Agẹmo 2026
Wo dúkìá 45 tó jẹ́ ti agbẹjọ́rò àgbà l'bẹ́ ìjọba Buhari, Abubakar Malami tí ilé ẹjọ́ gbẹ́sẹ̀lé
16 Agẹmo 2026
Page
1
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
40
Tókàn