BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ojude Ọba 2019: Àwọn èèkàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti péjú fún ayẹyẹ ojúde Ọba
Àkọlé àwòrán,
Ojude Oba tí ọdún yìí ti gbéra sọ pẹ̀lú oníruuru àwọn aṣọ alárànbara yorùba to ń wúni lóri, Awọn ẹgbẹ́ Tobalàṣẹ obinrin rèé nínú àṣọ okè aláwọ̀ ewé
Published
13 Ògún 2019
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀'
Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé
Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà
Ẹ ṣe àwárí ọdànran tó bọ mọ́ọ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Àkọlé àwòrán,
Lẹ́gbẹ́ lẹ́gbẹ́ ni gbogbo àwọn ti wọ́n péju síbi ayéyé Ojude Oba tí ọdún 2019
Àkọlé àwòrán,
Tokùnrin tobinrin ló wọsọ ìgbà níbi àyẹyẹ ojude oba tọdún yìí, Ẹgbẹ́ Bọbakẹ́yẹ Ọkunrin ni àwọn yìí
Àkọlé àwòrán,
Tarúgbó tomidàn ló wà nibi àyẹyẹ yìí, gbogbo oju wọ́n lo gúrégé pèlú, àwọn ẹgbẹ́ bọ́bakẹ́yẹ obinrin rèé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn olóyè àti èèkàn ìlú ló péjú
Àkọlé àwòrán,
Kìí ṣe àwọn ẹgbẹ́ gbẹ́ jọdá nìkàn ló péju, àwọn ọdọ náà jáde wá láti yẹ́ àṣ]a ìbílẹ̀ sí
Àkọlé àwòrán,
Aláàfin Ọyọ, ikú bábá yèyé, Ọba Lamidi Adeyemi náà péjú síbi ayẹyẹ ojúde Oba ní'lú Ijebu
Àkọlé àwòrán,
Gómínà ìpínlẹ̀ Ogun, Dapo Abiodun àti Awùjalẹ̀ Ijẹ̀bú Ọba Sikiru Adetona
Àkọlé àwòrán,
Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ogun, Ọtunba Gbẹnga Daniels
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Bọ́baguntẹ ilẹ̀ Ijẹbu
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo ojú tó ti ríra típẹ tún ni àànfàni láti ṣe "Ẹ k;u àti"
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Obafunwaji Obinrin Adedoyin rèé nínú aṣọ ofi aláwọ̀ búlù
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Tobalaṣẹ Ọkunrin náà ko gbẹ́yìn
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Fo Móríwú kọjá kí o tẹ̀síwájú
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
05:26
Fídíò,
Àwọn dókítà ti sọ fún mi pé kí n dẹ́kun sígà fífà àti ọtí mímu-Tope Osoba. Nibo Laye Koju Si?
, Duration 5,26
02:30
Fídíò,
Nǹkan kan tí mo mọ̀ ni pé bí orin tí mo bá kọ bá bùkún fún mi, yóò bùkún fún gbogbo èèyàn tó bá gbọ́ ọ - Bisi Manuel
, Duration 2,30
03:24
Fídíò,
Àwọn olólùfẹ́ Kola Oyewo sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ lẹ́yìn ìsìnkú rẹ̀
, Duration 3,24
04:02
Fídíò,
Àwọn sinimá kan wà tí mo ṣe tí àwọn òbí mi kò lè wò nítorí… - Bolaji Ogunmola, òṣèré tíátà
, Duration 4,02
02:58
Fídíò,
Ghana must go: Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa báàgì yìí àti bó ṣe gbajúmọ̀ ní Naijiria
, Duration 2,58
04:47
Fídíò,
"Àgọ́ NYSC ni mo ti ń bọ̀, tí mo fi kò ìjàmbá, n kò le dá jókòó, rìn, sùn, yàgbẹ́ tàbí tọ̀, tí mo bá tún ayé wa, n kò ní sìnrú ìlú mọ́"
, Duration 4,47
03:38
Fídíò,
À ti tún àwọn ẹ̀rọ̀ BVAS wa ṣe láti dènà kí èèyàn kan lo káàdì ìdìbò ẹlòmíràn nínú ìdìbò gómìna l‘Osun - Alága INEC
, Duration 3,38
04:06
Fídíò,
Ìwà tí ọ̀pọ̀ ‘Marketer’ ń hù, kù díẹ̀ káà tó, àwọn òṣèré gbà pé wọ́n gbọdọ́ gbéra sílẹ̀ fún wọn láti dìde - Nike Peller
, Duration 4,06
02:29
Fídíò,
'Mo ti padà sí ẹsẹ̀ àárọ̀ lẹ́yìn tí mo sá kúrò ní South Africa'
, Duration 2,29
04:56
Fídíò,
Èmi àti Funke Akindele ò jà, ohun tó ṣẹlẹ̀ rèé tí ẹ kò fi rí wa pọ̀ - Kamo State
, Duration 4,56
01:54
Fídíò,
Rofiat Imuran, agbábọ́ọ̀lù Super Falcons sọ̀rọ̀ lórí àwọn ayò tuntun tí Nàìjíríà yóò tun fi tayọ ní WAFCON ọdún yìí
, Duration 1,54
05:16
Fídíò,
Àdó olóró àwọn ajínigbé pa Shuaibu aṣọ́gbóọba lásìkò tó ń lé àwọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ gbé ní Oriire, àwọn ẹbí rẹ̀ pariwo síta
, Duration 5,16
02:35
Fídíò,
Wo ewu tó wà nínú kí èèyàn máa fi ẹsẹ̀ lásán rìn tàbí gbé bàtà tí o bá wọ́ jáde, wọnú ilé padà
, Duration 2,35
Ìparí Móríwú
Ìròyìn tó ṣe kókó
Èyí ni àkójopọ̀ èsì ìdìbó gómìnà láti ìpínlẹ̀ Osun
ìṣẹ́jú 30 sẹ́yìn
NÍ YÀJÓYÀJÓ
,
Àkójọpọ̀ ìròyìn bó ṣe ń lọ nínú ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Osun
Afurasí tó gún ₦56.4m owó Hajj tó gbà lọ́wọ́ àwọn èèyàn lọ́bẹ n'Ibadan fojú ba ilé ẹjọ́
wákàtí 6 sẹ́yìn
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Wó kókó méjìlá tó yẹ kí o mọ̀ nípa Temitope Osoba, òṣèré tíátà tó jáde láyé
6 Ògún 2026
Bíi ẹni tó ṣòwò tí kò jèrè ni ikú Tope Osoba jẹ́ -Foluke Daramola
12 Ògún 2026
Ọmogun Naijiria dóòlà èrò ọkọ̀ 33 lọ́wọ́ ajínigbé, bẹ́ sínú igbó láti fọ́wọ́ òfin máwọn jàndùkú agbébọn náà
9 Ògún 2026
Wo kókó ohun márùn-ún tó ń fa àìgbọ́raẹniyé láàárín tọkọtaya
9 Ògún 2026
Nítorí ìjà ilẹ̀ àti ìdigunjalè, èèyàn mẹ́wàá bọ́ sọ́wọ́ ọlọ́pàá l'Ondo
9 Ògún 2026
Wo àwọn ibi tí Egúngún Olóòlù yóò lọ nílùú Ibadan, àwọn ọjọ́ tí yóò wà láwọn agbègbè náà àti ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Egúngún olóòlù
28 Agẹmo 2026
Ilé tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ń gbé dàwó, èèyàn méjì kú, mẹ́ta dèrò ilé ìwòsàn
27 Agẹmo 2026
Baálé ilé fi ìyàwó àtàwọn ìbejì tí wọ́n bí sílẹ̀ ní South Africa, sá wá sí Nàìjíríà, àlàyé rẹ̀ rèé
8 Ògún 2026
Aláboyún méje bí ọmọ kú lọdọ̀ ajínigbé, márùn-ún gbé ọmọ wálé, àgbàdo àti iyọ̀ lóunjẹ wa lẹ́ẹ̀kan lọ́júmọ́ - Àwọn èèyàn ìlú Wọrọ tó gba ìdáǹde lọ́wọ́ ajínigbgbé sọ̀rọ̀
8 Ògún 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
NÍ YÀJÓYÀJÓ
Àkójọpọ̀ ìròyìn bó ṣe ń lọ nínú ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Osun
2
Èyí ni àkójopọ̀ èsì ìdìbó gómìnà láti ìpínlẹ̀ Osun
3
Pásítọ̀ Olùdásílẹ̀ ìjọ Ọlọ́run ṣàlàyé ìdí tó fi fẹ̀sìn Kristẹni sílẹ̀ di oníṣẹ̀ṣe tó sí pa orúkọ dà láti Felix sí Ifawamiri
4
Afurasí tó gún ₦56.4m owó Hajj tó gbà lọ́wọ́ àwọn èèyàn lọ́bẹ n'Ibadan fojú ba ilé ẹjọ́
5
Akẹ́kọ̀ọ́ FGC Yauri mẹ́ta pàdánù ẹ̀mí wọ́n nígbà t'awọn ológun àti ajínigbe kojú ará wọ́n
Tí a mú dójú ìwọ̀n gbẹ̀yìn ní: 30 Ẹrẹ̀nà 2020
6
Àwọn ọmọ gbajúmọ̀ akọrin Juju St. Janet ṣàlàyé ohun tó ṣekúpa gbajúgbajà Olórin náà
7
Olùdìbò 1.9m ni wọ́n ti n gbaradì fún ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Osun – INEC
8
Makinde lóùn ṣetán láti ṣàtúntò Nàíjíríà lọ́dún 2027
9
Òní lòní n jẹ́ nibi ètò òdun Sango tó ń wáyé nílùú Oyo Alaafin....
10
Ìjọ Mímọ́ CCC bẹ̀rẹ̀ ìwádìí ẹ̀sùn táwọn èèyàn fi kan Olùṣọ́ ọ̀rẹ́kùnrin Tope Osoba lóri ohun tó ṣokùnfà ikú rẹ̀